Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

“Jẹ́ Onígboyà àti Alágbára Kí O Sì Gbé Ìgbésẹ̀”!

Ó gba kéèyàn ní ìgbọ́kànlé nínú Jèhófà kó tó lè kojú àwọn ìṣòro. A máa rí bí ìgbọ́kànlé tí Dáfídì ní ṣe mú kó gbé ìgbésẹ̀.

A gbé e ka 1 Kíróníkà 28:1-20; 1 Sámúẹ́lì 16:1-23; 17:1-51

 

O Tún Lè Wo

ILÉ ÌṢỌ́

“Ti Jèhófà Ni Ìjà Ogun Náà”

Kí ló ran Dáfídì lọ́wọ́ láti pa Gòláyátì? Kí la rí kọ́ látinú ìtàn Dáfídì?