Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Ìwé Ìròyìn Ilé Ìṣọ́ àti

Àwọn ìwé ìròyìn wa tá a gbé ka Bíbélì wà lórí Íńtánẹ́ẹ̀tì, o lè wà wọ́n jáde ní ọgọ́rọ̀ọ̀rún èdè, èdè àwọn adití náà wà níbẹ̀. Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ ń jẹ́ ká rí bí àwọn àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì ṣe ń nímùúṣẹ lóde òní. Ó ń fi ìhìn rere Ìjọba Ọlọ́run tu àwọn èèyàn nínú, ó sì ń jẹ́ kéèyàn túbọ̀ nígbàgbọ́ nínú Jésù Kristi. Ìwé ìròyìn Jí! ń jẹ́ ká mọ bá a ṣe lè kápá àwọn ìṣòro òde òní, ó sì ń mú kéèyàn túbọ̀ gbà pé Ẹlẹ́dàá wa máa mú ayé tuntun wá, níbi tí alálàáfíà àti ààbò máa wà, gẹ́gẹ́ bó ṣe ṣèlérí.

Yan èdè tó o bá fẹ́ nínú àpótí kékeré tá a ti ń yan èdè, lẹ́yìn náà kó o tẹ Wá a, tó o bá ti tẹ̀ ẹ́, wà á rí àwọn ìwé ìròyìn ní oríṣiríṣi ọ̀nà.

 

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

February 2024

Àwọn àpilẹ̀kọ tá a máa kẹ́kọ̀ọ́ láti April 8–May 5, 2024 ló wà nínú Ilé Ìṣọ́ yìí.

ILÉ ÌṢỌ́

Ibo La Ti Lè Rí Òtítọ́?

Bíbélì sọ ìdáhùn tó jóòótọ́ nípa àwọn ìbéèrè pàtàkì tá a máa ń béèrè.

WÒ Ó

JÍ!

JÍ!

JÍ!

JÍ!

JÍ!

ILÉ ÌṢỌ́

ILÉ ÌṢỌ́

ILÉ ÌṢỌ́

ILÉ ÌṢỌ́

ILÉ ÌṢỌ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́